CALLED TO SHOW MERCY
THE SEED
“…To act justly and to love mercy and to walk humbly with your God.” — Micah 6:8b NIV
God requires three things of us: to act, to love, and to walk with Him. These are the foundations of Christian character. When
we have received God’s grace, blessings, and mercy, we must extend the same to care during the pandemic, we too must be channels of mercy and justice. What we do for others, we do for Christ. (Matthew 25:40) God expects more from those He has
blessedabundantly.
BIBLE READINGS: Micah 6:6–8
PRAYER: Father, help me to be a messenger of Your love and mercy, bringing hope to those in need. Amen.
ÌPÈ LÁTI FI ÀÁNÚ HÀN
IRUGBIN NAA
“Kí ó ṣé otitọ, kí ó sí fẹ́ àánú, àti kí ó rín ni irẹlẹ pèḷú Ọlóṛ un rẹ” MÍKÀ 6:8b.
Ohun mẹ́ta ni Ọlọ́run ń béèrè lọ́wọ́ wa: láti ṣe, láti ní ifẹ̀, àti láti bá a rìn. Iwọnyi jẹ awọn ipinlẹ iwa Kristiani. Nigba ti a ba ti gba oore-ọfẹ, awọn ibukun, ati aanu Ọlọrun, a gbọdọ na ọwọ́ àǹfààní bẹ ẹ si awọn miiran. Bi i awọn wọnni ti wọn fi ifẹ ati abojuto han lakoko ajakalẹ-arun, awa pẹlu gbọdọ jẹ ipa
ọna fun aanu ati idajọ ododo. Ohun ti a ṣe fun ẹlòmíràn, a ṣe fun Kristi. ( Mátíù 25:40 )
Ọlọ́run nretí púpọ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn tó ti bùkún fun lọ́pọ̀lọpọ̀.
BIBELI KIKA: Míkà 6:6–8
ADURA: Baba, ràn mi lọwọ lati jẹ Iranṣẹ ifẹ ati aanu Rẹ, ti yio mú ireti wa fun awọn ti o ṣe alaini. Amin.